Numbers 24:20 — Compare Translations

3 translations compared side by side

Yoruba 2010
Nígbà tí ó wo Amaleki, ó fi òwe sọ̀rọ̀ nípa wọn báyìí pé: “Amaleki ni orílẹ̀-èdè tí ó lágbára jùlọ, Ṣugbọn yóo ṣègbé níkẹyìn.”
Yoruba YBCV (Bibeli Mimọ)
Nigbati o si wò Amaleki, o si bẹ̀rẹsi owe rẹ̀, o si wipe, Amaleki ni ekini ninu awọn orilẹ-ède; ṣugbọn igbẹhin rẹ̀ ni ki o ṣegbé.
Yoruba YCB (Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní)
Nígbà náà ni Bálámù rí Ámálékì ó sì bẹ̀rẹ̀ òwe: “Ámálékì ni àkọ́kọ́ nínú àwọn orílẹ̀ èdè, ṣùgbọ́n yóò dahoro níkẹyìn.”