Awọn ọkunrin ti a pè li orukọ na si dide, nwọn si mu awọn igbekun na, nwọn si fi ikogun na wọ̀ gbogbo awọn ti o wà ni ihoho ninu wọn, nwọn si wọ̀ wọn laṣọ, nwọn si bọ̀ wọn ni bàta, nwọn si fun wọn ni ohun jijẹ ati ohun mimu, nwọn si fi ororo kùn wọn li ara, nwọn si kó gbogbo awọn alailera ninu wọn sori kẹtẹkẹtẹ, nwọn si mu wọn wá si Jeriko, ilu ọlọpẹ si ọdọ arakunrin wọn: nigbana ni nwọn pada wá si Samaria.
What Does This Mean?
In this verse, some men helped rescued captives by giving them clothes, food, drink, and care. They took care of the weak and brought them to Jericho. This shows the kindness and compassion of those who helped.
Explained for Children
Imagine if your friends got lost in the woods, and you found them cold and hungry. You would give them your snacks, warm them up with a blanket, and help them find their way home. That's what these nice men did for those who were captured.
Historical Background
2 Chronicles was written by an unknown author and is part of the historical books of the Old Testament, likely compiled between the 5th and 3rd centuries BC. This verse describes a historical event where captives were returned to their homes, and it was written for the Israelites to remember their history and God's actions.
Living It Out Today
Imagine if you saw someone who had lost their job and was struggling to afford basic needs. This verse encourages us to help them by providing food, clothes, and support, just like these men did for the captives.