bible
ra
🌐 Language
English
Español
Français
Deutsch
Português
Italiano
Nederlands
Русский
中文
日本語
한국어
العربية
Türkçe
Tiếng Việt
ไทย
Indonesia
All Languages
Home
/
Yoruba
/
Yoruba 2010
/
Ezekiel 19
Ezekiel 19
Yoruba 2010
← Chapter 18
Jump to:
Chapter 1
Chapter 2
Chapter 3
Chapter 4
Chapter 5
Chapter 6
Chapter 7
Chapter 8
Chapter 9
Chapter 10
Chapter 11
Chapter 12
Chapter 13
Chapter 14
Chapter 15
Chapter 16
Chapter 17
Chapter 18
Chapter 19
Chapter 20
Chapter 21
Chapter 22
Chapter 23
Chapter 24
Chapter 25
Chapter 26
Chapter 27
Chapter 28
Chapter 29
Chapter 30
Chapter 31
Chapter 32
Chapter 33
Chapter 34
Chapter 35
Chapter 36
Chapter 37
Chapter 38
Chapter 39
Chapter 40
Chapter 41
Chapter 42
Chapter 43
Chapter 44
Chapter 45
Chapter 46
Chapter 47
Chapter 48
Chapter 20 →
1
OLUWA ní kí n sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn nítorí àwọn olórí Israẹli,
2
kí n sọ pé: Abo kinniun pataki ni ìyá rẹ láàrin àwọn kinniun! Ó dùbúlẹ̀ láàrin àwọn ọ̀dọ́ kinniun, ó ń tọ́jú àwọn ọmọ rẹ̀.
3
Ó tọ́ ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà; ó di ọ̀dọ́ kinniun. Ó kọ́ ọ bí wọ́n tí ń ṣe ọdẹ, ó sì ń pa eniyan jẹ.
4
Àwọn eniyan ayé gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n tàn án sinu kòtò wọn. Wọ́n fi ìwọ̀ kọ́ ọ nímú, wọ́n sì fà á lọ sí ilẹ̀ Ijipti.
5
Nígbà tí abo kinniun náà rí i pé ọwọ́ tẹ ọmọ òun, ati pé igbẹkẹle òun ti dòfo, ó mú òmíràn ninu àwọn ọmọ rẹ̀, ó tọ́ ọ di ọ̀dọ́ kinniun.
6
Ó ń yan kiri láàrin àwọn kinniun; nítorí ó ti di ọ̀dọ́ kinniun tí ó lágbára, ó kọ́ bí wọn tí ń ṣe ọdẹ, ó sì ń pa eniyan jẹ.
7
Ó wó ilé ìṣọ́ wọn lulẹ̀; ó sọ ìlú wọn di ahoro. Ẹ̀rù ba gbogbo Ilẹ̀ náà, ati gbogbo àwọn tí ń gbé ibẹ̀, nígbà tí wọ́n gbọ́ bíbú rẹ̀.
8
Àwọn orílẹ̀-èdè bá dójú lé e, wọ́n dẹ tàkúté fún un ní gbogbo ọ̀nà, wọ́n da àwọ̀n wọn bò ó, wọ́n sì mú un ninu kòtò tí wọn gbẹ́ fún un.
9
Wọ́n sọ ìwọ̀ sí i nímú, wọ́n gbé e jù sinu àhámọ́, wọ́n sì fà á lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babiloni. Wọ́n fi sí àtìmọ́lé, kí wọ́n má baà gbọ́ ohùn rẹ̀ mọ́ lórí àwọn òkè Israẹli.
10
Ìyá rẹ dàbí àjàrà inú ọgbà tí a gbìn sí ẹ̀gbẹ́ odò; ó rúwé, ó yọ ẹ̀ka, nítorí ó rí omi lọpọlọpọ.
11
Ẹ̀ka rẹ̀ tí ó lágbára ni a fi gbẹ́ ọ̀pá àṣẹ fún àwọn olórí. Ó dàgbà, ó ga fíofío, láàrin àwọn igi igbó. Ó rí i bí ó ti ga, tí ẹ̀ka rẹ̀ sì pọ̀.
12
Ṣugbọn a fa àjàrà náà tu pẹlu ibinu, a sì jù ú sílẹ̀. Afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn mú kí ó gbẹ, gbogbo èso rẹ̀ sì rẹ̀ dànù. Igi rẹ̀ tí ó lágbára gbẹ, iná sì jó o.
13
Nisinsinyii, a ti tún un gbìn sinu aṣálẹ̀, ninu ilẹ̀ gbígbẹ níbi tí kò sí omi.
14
Iná ṣẹ́ lára igi rẹ̀, ó sì jó gbogbo ẹ̀ka ati èso rẹ̀. Kò sì ní igi tí ó lágbára mọ́, tí a lè fi gbẹ́ ọ̀pá àṣẹ fún ọba. Dájúdájú ọ̀rọ̀ arò ni ọ̀rọ̀ yìí, ó sì ti di orin arò.
← Chapter 18
Jump to:
Chapter 1
Chapter 2
Chapter 3
Chapter 4
Chapter 5
Chapter 6
Chapter 7
Chapter 8
Chapter 9
Chapter 10
Chapter 11
Chapter 12
Chapter 13
Chapter 14
Chapter 15
Chapter 16
Chapter 17
Chapter 18
Chapter 19
Chapter 20
Chapter 21
Chapter 22
Chapter 23
Chapter 24
Chapter 25
Chapter 26
Chapter 27
Chapter 28
Chapter 29
Chapter 30
Chapter 31
Chapter 32
Chapter 33
Chapter 34
Chapter 35
Chapter 36
Chapter 37
Chapter 38
Chapter 39
Chapter 40
Chapter 41
Chapter 42
Chapter 43
Chapter 44
Chapter 45
Chapter 46
Chapter 47
Chapter 48
Chapter 20 →
All chapters:
1
2
3
4
5
6
7
8
9
10
11
12
13
14
15
16
17
18
19
20
21
22
23
24
25
26
27
28
29
30
31
32
33
34
35
36
37
38
39
40
41
42
43
44
45
46
47
48