bible
ra
🌐 Language
English
Español
Français
Deutsch
Português
Italiano
Nederlands
Русский
中文
日本語
한국어
العربية
Türkçe
Tiếng Việt
ไทย
Indonesia
All Languages
Home
/
Yoruba
/
Yoruba 2010
/
Isaiah 31
Isaiah 31
Yoruba 2010
← Chapter 30
Jump to:
Chapter 1
Chapter 2
Chapter 3
Chapter 4
Chapter 5
Chapter 6
Chapter 7
Chapter 8
Chapter 9
Chapter 10
Chapter 11
Chapter 12
Chapter 13
Chapter 14
Chapter 15
Chapter 16
Chapter 17
Chapter 18
Chapter 19
Chapter 20
Chapter 21
Chapter 22
Chapter 23
Chapter 24
Chapter 25
Chapter 26
Chapter 27
Chapter 28
Chapter 29
Chapter 30
Chapter 31
Chapter 32
Chapter 33
Chapter 34
Chapter 35
Chapter 36
Chapter 37
Chapter 38
Chapter 39
Chapter 40
Chapter 41
Chapter 42
Chapter 43
Chapter 44
Chapter 45
Chapter 46
Chapter 47
Chapter 48
Chapter 49
Chapter 50
Chapter 51
Chapter 52
Chapter 53
Chapter 54
Chapter 55
Chapter 56
Chapter 57
Chapter 58
Chapter 59
Chapter 60
Chapter 61
Chapter 62
Chapter 63
Chapter 64
Chapter 65
Chapter 66
Chapter 32 →
1
Àwọn tí ó ń lọ sí Ijipti fún ìrànlọ́wọ́ gbé! Àwọn tí wọ́n gbójú lé ẹṣin; tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé kẹ̀kẹ́ ogun nítorí pé wọ́n pọ̀, tí wọ́n gbójú lé ẹṣin nítorí pé wọ́n lágbára! Wọn kò gbójú lé Ẹni Mímọ́ Israẹli, wọn kò sì wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ OLUWA.
2
Bẹ́ẹ̀ ni ó gbọ́n, ó sì mọ ọ̀nà tí ó fi lè mú kí àjálù dé bá eniyan, kì í sọ̀rọ̀ tán, kó yí ọ̀rọ̀ rẹ̀ pada. Ṣugbọn yóo dìde sí ìdílé àwọn aṣebi, ati àwọn tí ń ti àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ lẹ́yìn.
3
Eniyan sá ni àwọn ará Ijipti, wọn kìí ṣe Ọlọrun. Ẹranko lásán sì ni ẹṣin wọn wọn kì í ṣe àǹjọ̀nnú. Bí OLUWA bá na ọwọ́, tí ó bá gbá wọn mú, ẹni tí ń ranni lọ́wọ́ yóo fẹsẹ̀ kọ, ẹni tí à ń ràn lọ́wọ́ yóo ṣubú; gbogbo wọn yóo sì jọ ṣègbé pọ̀.
4
Nítorí OLUWA sọ fún mi pé, “Bí kinniun tabi ọmọ kinniun ti máa ń kùn lórí ẹran tí ó bá pa, tí kìí bìkítà fún igbe àwọn olùṣọ́ aguntan, tí wọ́n pera wọn jọ, tí wọn ń bọ̀, tí ẹ̀rù ariwo wọn kìí sìí bà á; bẹ́ẹ̀ ni OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo sọ̀kalẹ̀, yóo wá jà lórí òkè Sioni ati àwọn òkè tí ó yí Sioni ká.
5
Bí àwọn ẹyẹ tií da ìyẹ́ bo ìtẹ́ wọn, bẹ́ẹ̀ ni OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo dáàbò bo Jerusalẹmu, yóo dáàbò bò ó, yóo sì gbà á sílẹ̀ yóo dá a sí, yóo sì yọ ọ́ kúrò ninu ewu.”
6
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ pada sọ́dọ̀ ẹni tí ẹ ti ṣàìgbọràn sí lọpọlọpọ.
7
Nítorí pé ní ọjọ́ náà, olukuluku yóo gbé àwọn ère fadaka ati ère wúrà tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ ṣe sọnù, àwọn ère tí ó mú wọn dẹ́ṣẹ̀.
8
Idà ni yóo pa Asiria, ṣugbọn kì í ṣe láti ọwọ́ eniyan; idà tí kò ní ọwọ́ eniyan ninu ni yóo pa á run. Yóo sá lójú ogun, a óo sì kó àwọn ọmọkunrin rẹ̀ lọ máa ṣiṣẹ́ tipátipá.
9
Ẹ̀rù yóo ba ọba Asiria, yóo sálọ. Ìpayà yóo mú kí àwọn ọ̀gágun rẹ̀ ju àsíá sílẹ̀. OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀, OLUWA tí iná rẹ̀ wà ní Sioni, tí ojú ààrò rẹ̀ wà ní Jerusalẹmu.
← Chapter 30
Jump to:
Chapter 1
Chapter 2
Chapter 3
Chapter 4
Chapter 5
Chapter 6
Chapter 7
Chapter 8
Chapter 9
Chapter 10
Chapter 11
Chapter 12
Chapter 13
Chapter 14
Chapter 15
Chapter 16
Chapter 17
Chapter 18
Chapter 19
Chapter 20
Chapter 21
Chapter 22
Chapter 23
Chapter 24
Chapter 25
Chapter 26
Chapter 27
Chapter 28
Chapter 29
Chapter 30
Chapter 31
Chapter 32
Chapter 33
Chapter 34
Chapter 35
Chapter 36
Chapter 37
Chapter 38
Chapter 39
Chapter 40
Chapter 41
Chapter 42
Chapter 43
Chapter 44
Chapter 45
Chapter 46
Chapter 47
Chapter 48
Chapter 49
Chapter 50
Chapter 51
Chapter 52
Chapter 53
Chapter 54
Chapter 55
Chapter 56
Chapter 57
Chapter 58
Chapter 59
Chapter 60
Chapter 61
Chapter 62
Chapter 63
Chapter 64
Chapter 65
Chapter 66
Chapter 32 →
All chapters:
1
2
3
4
5
6
7
8
9
10
11
12
13
14
15
16
17
18
19
20
21
22
23
24
25
26
27
28
29
30
31
32
33
34
35
36
37
38
39
40
41
42
43
44
45
46
47
48
49
50
51
52
53
54
55
56
57
58
59
60
61
62
63
64
65
66